a
Mk 3.7-12
;
Lk 6.17-19
.
Matthew 12:15-16
Ìránṣẹ́ tí Ọlọ́run yàn
15
a
Nígbà tí Jesu sì mọ̀, ó yẹra kúrò níbẹ̀. Ọ̀pọ̀ ìjọ ènìyàn sì ń tọ̀ ọ́ lẹ́yìn, ó sì mú gbogbo àwọn aláìsàn láradá.
16
Ṣùgbọ́n ó kìlọ̀ fún wọn pé kí wọ́n kí ó má ṣe fi òun hàn.
Copyright information for
YorBMYO